Iwoye: Àwọn ọlọ́pàá mú ènìyàn mẹ́ta ní ìlú Jos nítorí ikú Ibrahim ti won fi esun ole kan…
Ní ọ̀sẹ̀ yìí lórí Ìwòyé: Àwọn ọlọ́pàá mú ènìyàn mẹ́ta ní ìlú Jos nítorí ikú Ibrahim to win fi esun ole kan; wọ́n tún mú awakọ̀ kan ní Ìjẹ̀bú-Òde, nítorí ìjàmbá tí wọ́n ní ó mọ̀ọ́mọ̀ fà, tó sì ṣokùnfà ikú arìnrìn-àjò kan; wọ́n sì mú onigbajamo kan ní Ìpínlẹ̀ Abíà lórí ẹ̀sùn lílo irun […]

